BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Orilẹede Naijiria
0:54
Orin,
Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
, Duration 0,54
1 Owewe 2026
Gbàjarè oo! Inú àpò àṣùwọ̀n owó orí ayélujára 'crypto' ni wọ́n n jí owó ìjọba ìbílẹ̀ pamọ́ sí báyìí – EFCC figbe ta
1 Owewe 2026
Àlàyé rèé lórí ipa táwọn ikọ̀ aláàbò kó lórí báwọn Àgùnbánirọ̀ mẹ́ẹ̀dógún, aráàlú mẹ́fa, tí wọn jí gbé ní Kogi, ṣe gba ìtúsílẹ̀ àti ohun tí ààrẹ Tinubu sọ
1 Owewe 2026
Ṣé lóòótọ́ ni OPay fẹ́ kógbá wọlé ní Naijiria lónìí ọjọ́ kíní oṣù Kẹ́sàn án? Ohun tí a mọ̀ rèé
1 Owewe 2026
Ìdí rèé tí Dangote fi ṣe àfikún owó epo bẹntiróòlù fún ìgbà mẹ́ta láàrin ọ̀sẹ̀ kan àti ipa rẹ̀ lórí aráàlú
31 Ògún 2026
Ta ló ń pààrọ̀ orúkọ àwọn olùdíje ẹgbẹ́ òṣèlú NDC lójú òpó àjọ elétò ìdìbò, bí INEC ṣe sẹ́ pé òun kọ́?
31 Ògún 2026
4:55
Fídíò,
Ẹlẹ́mí èṣù làwọn ayálégbé míràn, àfi kí ìjọ̀ba yọwọ́ lọ́rọ́ onílé àti ayálégbé ní Nàìjíríà – Isaac Fayose
, Duration 4,55
29 Ògún 2026
Wo ọ̀nà àrékérekè tuntun táwọn agbésùnmọ̀mí ń gbà r'owó ní Naijiria bàyìí yàtọ̀ sí gbígba owó ìtúsílẹ̀
29 Ògún 2026
Wo àwọn ohun tó ṣẹlẹ̀ ṣáájú ìkọ̀wéfipòsílẹ̀ Ààrẹ NFF, Ibrahim Gusau
28 Ògún 2026
4:03
Fídíò,
Àwọn 'ọlọ́pàá' tó fẹ́ wá fi tipá gbé mi gbá ìdí ìbọn gbá ìyàwó mi, wọ́n sì bá oyún inú rẹ̀ jẹ́ – Tani Olohun
, Duration 4,03
28 Ògún 2026
Ọmọ ọdún 90 ni Ààrẹ Tinubu, Ó sì ń ṣàárẹ̀, ẹ̀rí tó dájú ń bẹ lọ́wọ́ mi - Atiku Abubakar, olùdíje ADC
28 Ògún 2026
Ṣé lóòótọ́ ni Kira, ọmọ Ogogo bímọ tuntun? Mọ̀lẹ́bí Ogogo sọ̀rọ̀ síta
28 Ògún 2026
Bí o ṣe lè di olówó gọbọi nípa títú àṣírí àwọn tó ń jí owó ìlú kó lọ sókè òkun
27 Ògún 2026
Bílíọ̀nù mẹ́jọ Naira làwọn ajínigbé ti gbà lọ́wọ́ aráàlú láàrín ọdún 2025 sí 2026 - Ìwádìí
27 Ògún 2026
3:13
Fídíò,
Obìnrin tó bá fẹ́ fẹ́ mi gbọ́dọ̀ ṣetán láti san owó orí mi – VJ Adams
, Duration 3,13
27 Ògún 2026
Ọlọ́pàá ṣàwárí ilé tí wọ́n ti ń ta ọmọ ní Mowe, tú àwọn olóyún àti ọmọdé sílẹ̀
26 Ògún 2026
Àwọn ọlọ́jà ní àwọn kan ló mọ́ọ̀mọ̀ sọná sọ́jà Oranyan ní Ibadan, pè fún ìwádìí látọ̀dọ̀ ìjọ̀ba, Sarafadeen Alli ṣèlérí ìrànwọ́
25 Ògún 2026
5:13
Fídíò,
Òṣìṣẹ́ báǹkì tó di ẹni tó ń ta pọ̀nmọ́ aláta lọ́jà nílùú Ibadan
, Duration 5,13
25 Ògún 2026
A sa gbogbo ipá wa láti gba ẹ̀mí Ogogo là – Yayi
24 Ògún 2026
Òkú sùn, dúkìá ọ̀pọ̀lọpọ̀ mílíọ̀nù bàjẹ́ lásìkò táwọn awakọ̀èrò gbìyànjú láti gba gáréèjì ní Ikire
24 Ògún 2026
Wo ìdí tí ìjọba Nàìjíríà fi kéde ìsinmi lẹ́nu iṣẹ́ lọ́jọ́ Ìṣẹ́gun
24 Ògún 2026
Ṣé òótọ́ ni ìjọba ìpínlẹ̀ Edo ti fòfin de Davido láti má wọ ìpínlẹ̀ náà mọ́? Gómìnà Okpebholo ṣàlàyé
23 Ògún 2026
Ọwọ́ NDLEA tẹ ìyá àgbà ẹni ọdún 101 tó ń ta oògùn olóró ní ìpínlẹ̀ Ogun
23 Ògún 2026
Obi Cubana fi ilé ńlá ta gbajúmọ̀ pásítọ̀, Jerry Eze, lọ́rẹ bíi ẹ̀bùn ọjọ́ọ̀bí ọdún kẹrìnlélógójì
23 Ògún 2026
Page
1
nínú
40
1
2
3
4
5
6
7
40
Tókàn