BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Gómìnà Adeleke, mo kí ẹ kú oríire pé o wọlé fún sáà kejì àmọ́ ọ̀rọ̀ sì kù lẹ́yìn rẹ̀ - Oyebamiji, olùdíje gómìnà APC l'Osun
Oyebamiji nigba to n ba awọn ọmọ ẹyin ati alatilẹyin rẹ sọrọ fun igba akọkọ lẹyin eto idibo naa, iyẹn lọjọ Abamẹta to kọja, lo ti sọ pe oniruuru aṣemaṣe lo waye lasiko eto idibo naa.
Wo ìdí pàtàkí mẹ́rin tí Ààrẹ Tinubu kò ṣe fẹ́ kí ilẹ̀ Amẹ́ríkà fí àkọsílẹ̀ rẹ̀ nípà egbòogi olóró síta
Ninu iwe naa ni wọn ti sọ pe ofin anfaani si iroyin ati idaabo bo ẹtọ ọmọniyan yẹ ko jọba lori ṣiṣe afihan awọn akọsilẹ wọn, ati pe ko sẹnikẹni to fẹẹ mọ nipa rẹ.
Kí ni àrùn Diphtheria tó pa ọmọdé méje ní Imo, tó tún mú kí ilé ìwòsàn kún fọ́fọ́ ní Katsina?
Gẹgẹ bi wọn ṣe sọ, ojojumọ lawọn obi n ko awọn ọmọ wọn to lugbadi arun naa wa sile iwosan ọhun bayii, ẹsẹ ko si gba ero mọ.
Gómìnà Adeleke gbé ìgbìmọ̀ dìde láti ṣe ìwádìí àwọn ìpànìyàn tó wáyé nílùú Ikire
Igbimọ oluwadii naa ti adajọ Majisireeti Ayokunle Shiyanbola ko sodi ni wọn yoo ṣewadii ohun to ṣokunfa ikọlu naa, ṣe agbejade iye ati orukọ awọn to fori sọta iṣẹlẹ naa, ṣewadii ohun to ikọlu ọhun ati boya o ni nnkan ṣe pẹlu iku to waye nibẹ.
Ìjọba Niger sọ̀rọ̀ lórí ìgbìyànjú láti dìtẹ̀gbàjọba tó wáyé
Niṣe ni iro ibọn n dun lakọlakọ, ti ado oloro si n dun kaakiri ni Niamey ni owurọ kutukutu ọjọ Abamẹta gẹgẹ bi awọn ti iṣẹlẹ naa ṣoju wọn ṣe sọ.
Wo ìdí mẹ́ta tí akẹ́kọ̀ọ́ tí ilé ẹ̀kọ́ ti gbà wọlè le má rìí orúkọ rẹ̀ lójú òpó JAMB àtàwọn ìgbésẹ̀ tò yẹ kó o gbé
JAMB ninu alaye kan ti wọn gbe soju opo ayelujara X wọn ṣalaye pe o ṣeeṣe ki eeyan ti ile ẹkọ to ṣe idanwo lati lọ gba a wọle amọ ki wọn ma ri loju opo JAMB pe wọn ti gba a sile ẹkọ naa ati pe awọn nnkan mẹta lo maa n ṣokunfa rẹ.
Fídíò, Ẹlẹ́mí èṣù làwọn ayálégbé míràn, àfi kí ìjọ̀ba yọwọ́ lọ́rọ́ onílé àti ayálégbé ní Nàìjíríà – Isaac Fayose, Duration 4,55
Ninu eto 'Nibo laye kọju si?' ti ọsẹ yii, eekan kan lawujọ, Isaac Fayose ni ko si ohun to yẹ ko kan ijọba nipa inọja laarin larinlọọdu ati ayalegbe.
Wo oúnjẹ méjìlá tó ń ran iṣẹ́ ọpọlọ àti ìròrí lọ́wọ́
Bi ọpọlọ ṣe jẹ kókó ohun ti ẹda fi n huwa, bẹẹ naa lo tun n kopa ninu idari ohun to n ṣẹlẹ ninu ara.
Àwọn mọ̀lẹ́bí àwọn tó kú níbí ìkọlù Ikire n bèèrè fín ìdájọ́ òdodo
Bi ẹ ko ba gbagbe, ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Osun ti sọrọ lori ohun to ṣokunfa ikọlu to da ẹmi awọn eeyan legbodo, ti wọn si sọ abajade iwadii ti wọn ṣe.
Èèyà mẹ́ta farapa níbi tí ọlọ́pàá ti yìnbọn pa awakọ̀ lásìkò àyẹ̀wò
Asiko ti wọn lawọn ọlọpaa da awakọ naa duro lati yẹ ẹ wo, ṣugbọn ti ko duro, ni wọn sọ pe ọkan lara awọn ọlọpaa naa yinbọn fun un, to si gbabẹ sọda sọrun alakeji ori irin.
Àìsàn jẹjẹrẹ kọlu àgbà òṣèrè mííràn
Dasofunjo rọ awọn ọkunrin kaakiri agbaye lati maa wa ni ikiyesara lori aisan jẹjẹrẹ to nii ṣe pẹlu nnkan ọmọkunrin, iyẹn prostrate cancer.
Wo ọ̀nà àrékérekè tuntun táwọn agbésùnmọ̀mí ń gbà r'owó ní Naijiria bàyìí yàtọ̀ sí gbígba owó ìtúsílẹ̀
ẹka kan to n ri si itọpinpin ibi towo n gba wọle, 'Nigeria Financial Intelligence Unit' (NFIU) ti sọ pe awọn agbebọn n fi ojoojumọ lekun si i nipa ọna ati maa rowo ṣiṣẹ laabi wọn ni.
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Ọmọ ọdún 90 ni Ààrẹ Tinubu, Ó sì ń ṣàárẹ̀, ẹ̀rí tó dájú ń bẹ lọ́wọ́ mi - Atiku Abubakar, olùdíje ADC
Atiku ni ọjọ ori aarẹ ju eyi to n polongo fun gbogbo aye lọwọ yii ati wi pe ilera rẹ ko gbe iṣẹ akoso orilẹede Naijiria mọ.
Awuyewuye tún bẹ́ sílẹ̀ lórí ìyọnípò olórí ilé aṣòfin Ondo
Iroyin fi kun pe awọn ọlọpaa lati olu ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Ondo lo tete ji giri sawọn janduku naa ki awọn aṣofin naa to le maa ba ipade wọn lọ.
Àlàyé lórí ohun tó fa gbas-gbos láàárín VDM àti iléeṣẹ́ ọlọ́pàá Naijiria
VDM sọ pe awọn ọlọpaa lo n ṣe agbodegba fun awọn ajinigbe atawọn janduku agbenipa ni Naijiria.
Ṣé lóòótọ́ ni Kira, ọmọ Ogogo bímọ tuntun? Mọ̀lẹ́bí Ogogo sọ̀rọ̀ síta
Iroyin ibi naa n waye lẹyin ọjọ diẹ si iku baba wọn eleyi to mu ki ọpọ fẹ mọ boya lotitọ ni iroyin naa.
Bí o ṣe lè di olówó gọbọi nípa títú àṣírí àwọn tó ń jí owó ìlú kó lọ sókè òkun
Alaga ajọ EFCC, Ola Olukoyede, lo sọrọ naa nibi ipade International Symposium on Economic Crime to waye ni Cambridge, nilẹ Gẹẹsi.
Tani Olohun ṣàlàyé ohun tó mú Sunday Igboho wá sílé rẹ̀, àti ọ̀rọ̀ tó bá ọ̀gá ọlọ́pàá Kwara sọ káwọn ọlọ́pàá tó wá fipá gbé e nílé tó lè kúrò lágbègbè rẹ̀
Ninu fidio ti Ta ni Oloun ṣe naa, eyi to ti so bandeeji mọ ọwọ to si fi yipo ọrun rẹ lo ti ni oun n gba itọju lọwọ latari bawọn ọlọpaa Kwara naa ṣe gídì oun.
Bílíọ̀nù mẹ́jọ Naira làwọn ajínigbé ti gbà lọ́wọ́ aráàlú láàrín ọdún 2025 sí 2026 - Ìwádìí
Ninu iwadii rẹ, o ni ẹgbẹ alakatakiti ẹsin Boko Haram lo gba ida aadọrun (90%) awọn owo itusilẹ ti wọn kọ silẹ lẹkun ila oorun Ariwa, bi o tilẹ jẹ wi pe iṣẹlẹ ijinigbe atawọn ti wọn ji gbe pọ ju tiwọn lọ lẹkun iwọ oorun ariwa orilẹede Naijiria.
Àwọn wo ni ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn 'Black Axe' tí ọlọ́pàá àgbáyé mú fún jìbìtì orí ayélujéra káàkiri àgbáyé àti ní ìwọ̀ oòrùn Africa? Àlàyé rèé
Awọn ọlọpaa Interpol mu awọn eeyan naa ninu iṣẹ kan ti wọn doju rẹ kọ awọn ẹgbẹ ọdaran kaakiri Iwọ-Oorun Africa (West Africa).
Àwọn ọmọ Africa wà nínú àwọn tí wọ́n ń wá níbi àjálù ilẹ̀ rírì tó ti gbẹ̀mí èèyàn tó lé ní 160 ní Nepal, èèyàn 800 míràn di àwátì
A gbọ pe ilẹ riri wọ awọn yẹpẹ to wa lara awọn oke kan sinu odo Bhote Koshi, eyii to mu ki odo naa ya wọ aarin ilu.
Ètò ìsìnkú ti bẹ̀rẹ̀ fún Taiwo Hassan 'Ogogo'
Ọmọọba Jide Kosoko lo fi ikede naa sita loju opo Facebok ati Instagram rẹ lorukọ mọlẹbi oloogbe ọhun.
Iná sọ níléèwòsàn, ọmọ ìkókó mẹ́rìnlá jóná mọ́lé
Ijamba ina naa bẹ silẹ ni aja kẹta ileewosan ọhun nibi ti wọọdu awọn obinrin atawọn ọmọde wa.
Ọlọ́pàá ṣàwárí ilé tí wọ́n ti ń ta ọmọ ní Mowe, tú àwọn olóyún àti ọmọdé sílẹ̀
Abule Abaren, ni Mowe ni ile naa wa gẹgẹ bi DSP Oluseyi Babaseyi, Alukoro ọlọpaa ipinlẹ Ogun ṣe wi ninu atẹjade to fi sita lọjọ Iṣẹgun.
Kọ́milẹ́kọ̀ọ́
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Wo àwọn òṣèré tíátà Yoruba méje tó jáde láyé lọ́dún 2026
Lara nnkan to gbẹmi awọn oṣere naa ni aisan, ijamba ọkọ, ati bẹẹ lọ.
Gbajúgbajà Akéwì asùnjálá ọdẹ, Alabi Ogundepo jade láyé, àwọn mọ̀lẹ́bí sọ̀rọ̀
Awọn mọlẹbi agba akewi, onkọwe ati onkọtan naa lo kede iku ọmọ bibi ilu Saki nipinlẹ Oyo ọhun lọjọ Aje, ọsẹ yii.
Kí ló dé tí ìjọba àpapọ̀ yọwọ́ Makinde kúrò níbi ìfilọ́lẹ̀ òpópónà Ibadan sí Ijebu-Ode? Ohun tí a mọ̀ rèé
Ijọba ipinlẹ Oyo jẹ ko di mimọ pe igbesẹ naa lo lọwọ oṣelu ninu, eyi ti wọn sọ pe ko lọ ni ibamu pẹlu eto oṣelu awa-ara-wa.
Òkú sùn, dúkìá ọ̀pọ̀lọpọ̀ mílíọ̀nù bàjẹ́ lásìkò táwọn awakọ̀èrò gbìyànjú láti gba gáréèjì ní Ikire
Gẹgẹbi ohun ti a gbọ, awọn ọmọ ẹgbẹ awakọ ero to wa labẹ igun kan naa ni wọn n ba ara wọn ja lori wi pe igun kan lo kan lati ṣe akoso ẹgbẹ naa.
Ṣé òótọ́ ni ìjọba ìpínlẹ̀ Edo ti fòfin de Davido láti má wọ ìpínlẹ̀ náà mọ́? Gómìnà Okpebholo ṣàlàyé
Fidio kan lori ayelujara lo kede pe wọn ti fofin de Davido lati ma ṣe wọ ipinlẹ Edo.
Àkìtàn ya bo ilé ní Guinea, pa èèyàn 31
Ọjọ Aiku ana ti i ṣe ọjọ kẹtalelogun oṣu Kẹjọ ọdun 2026 ni iṣẹlẹ naa waye, ni nnkan bii aago meji si mẹta oru, lẹyin ojo arọọda kan to rọ.
Obi Cubana fi ilé ńlá ta gbajúmọ̀ pásítọ̀, Jerry Eze, lọ́rẹ bíi ẹ̀bùn ọjọ́ọ̀bí ọdún kẹrìnlélógójì
Pastor Eze lo maa n sọ aṣayan ọrọ oyinbo kan to kari bayii, iyẹn 'What God Cannot Do Does Not Exist'. To tumọ si pe ko sohun ti Ọlọrun ko le ṣe.
Kà nípa àwọn gbajúmọ̀ mẹ́wàá tó ti lùgbàdì àìsàn Jẹjẹrẹ
Bo tilẹ jẹ pe awọn dokita sọ pe Jẹjẹrẹ ti a mọ si Cancer ki i ṣe idajọ iku bi eeyan ba tete mọ pe oun ti lugbadi ẹ, sibẹ, ọkan lara awọn aisan to n ja okun ẹmi eeyan ni.
Ìwádìí bẹ̀rẹ̀ lórí ikú tó pa mọ̀lẹ́bí mẹ́rin lẹ́yìn tí wọ́n jẹ àmàlà tán ní Kogi
Koda, aja ti idile naa n sin paapaa jade laye lẹyin to jẹ ninu amala to pa awọn olowo rẹ.












































































